Surah Hud Verse 17 - Yoruba Translation by Shaykh Abu Rahimah Mikael Aykyuni
Surah Hudأَفَمَن كَانَ عَلَىٰ بَيِّنَةٖ مِّن رَّبِّهِۦ وَيَتۡلُوهُ شَاهِدٞ مِّنۡهُ وَمِن قَبۡلِهِۦ كِتَٰبُ مُوسَىٰٓ إِمَامٗا وَرَحۡمَةًۚ أُوْلَـٰٓئِكَ يُؤۡمِنُونَ بِهِۦۚ وَمَن يَكۡفُرۡ بِهِۦ مِنَ ٱلۡأَحۡزَابِ فَٱلنَّارُ مَوۡعِدُهُۥۚ فَلَا تَكُ فِي مِرۡيَةٖ مِّنۡهُۚ إِنَّهُ ٱلۡحَقُّ مِن رَّبِّكَ وَلَٰكِنَّ أَكۡثَرَ ٱلنَّاسِ لَا يُؤۡمِنُونَ
Nje eni t’o n be lori eri t’o yanju lati odo Oluwa re (iyen, Anabi s.a.w.), ti olujerii kan (iyen, molaika Jibril) si n ke al-Ƙur’an (fun un) lati odo Allahu, ti tira (Anabi) Musa si ti wa siwaju re, ti o je tira ti won n tele, o si je ike (fun won), (nje Anabi yii jo olusina bi?) Awon (musulumi) wonyi ni won si gba a gbo ni ododo. Enikeni t’o ba sai gba a gbo ninu awon ijo (nasara, yehudi ati osebo), nigba naa Ina ni adehun re. Nitori naa, ma se wa ninu iyemeji nipa al-Ƙur’an. Dajudaju ododo ni lati odo Oluwa re, sugbon opolopo eniyan ni ko gbagbo