وَنَادَىٰ نُوحٞ رَّبَّهُۥ فَقَالَ رَبِّ إِنَّ ٱبۡنِي مِنۡ أَهۡلِي وَإِنَّ وَعۡدَكَ ٱلۡحَقُّ وَأَنتَ أَحۡكَمُ ٱلۡحَٰكِمِينَ
(Anabi) Nuh pe Oluwa re, o si so pe: “Oluwa mi, dajudaju omo mi wa ninu ara ile mi. Ati pe dajudaju adehun Re, ododo ni. Iwo l’O si mo ejo da julo ninu awon adajo
Author: Shaykh Abu Rahimah Mikael Aykyuni