وَقَضَيۡنَآ إِلَىٰ بَنِيٓ إِسۡرَـٰٓءِيلَ فِي ٱلۡكِتَٰبِ لَتُفۡسِدُنَّ فِي ٱلۡأَرۡضِ مَرَّتَيۡنِ وَلَتَعۡلُنَّ عُلُوّٗا كَبِيرٗا
A si fi mo awon omo ’Isro’il ninu Tira pe: “Dajudaju e maa sebaje lori ile nigba meji. Dajudaju e tun maa segberaga t’o tobi.”
Author: Shaykh Abu Rahimah Mikael Aykyuni