Surah Al-Baqara Verse 126 - Yoruba Translation by Shaykh Abu Rahimah Mikael Aykyuni
Surah Al-Baqaraوَإِذۡ قَالَ إِبۡرَٰهِـۧمُ رَبِّ ٱجۡعَلۡ هَٰذَا بَلَدًا ءَامِنٗا وَٱرۡزُقۡ أَهۡلَهُۥ مِنَ ٱلثَّمَرَٰتِ مَنۡ ءَامَنَ مِنۡهُم بِٱللَّهِ وَٱلۡيَوۡمِ ٱلۡأٓخِرِۚ قَالَ وَمَن كَفَرَ فَأُمَتِّعُهُۥ قَلِيلٗا ثُمَّ أَضۡطَرُّهُۥٓ إِلَىٰ عَذَابِ ٱلنَّارِۖ وَبِئۡسَ ٱلۡمَصِيرُ
(E ranti) nigba ti (Anabi) ’Ibrohim so pe: “Oluwa mi, se ilu yii ni ilu ifayabale. Ki O si pese awon eso fun awon ara ibe (iyen) enikeni ninu won ti o ba ni igbagbo ododo ninu Allahu ati Ojo Ikeyin.” (Allahu) so pe: "Ati eni ti o ba sai gbagbo, Emi yoo fun un ni igbadun die. Leyin naa, Mo maa taari re sinu iya Ina. Ikangun naa si buru