ٱلَّذِينَ إِذَآ أَصَٰبَتۡهُم مُّصِيبَةٞ قَالُوٓاْ إِنَّا لِلَّهِ وَإِنَّآ إِلَيۡهِ رَٰجِعُونَ
Awon ti (o je pe) nigba ti adanwo kan ba kan won, won a so pe: “Dajudaju Allahu l’O ni awa; dajudaju odo Re si ni awa yoo pada si.”
Author: Shaykh Abu Rahimah Mikael Aykyuni