۞وَأَيُّوبَ إِذۡ نَادَىٰ رَبَّهُۥٓ أَنِّي مَسَّنِيَ ٱلضُّرُّ وَأَنتَ أَرۡحَمُ ٱلرَّـٰحِمِينَ
(E ranti Anabi) ’Ayyub, nigba ti o pe Oluwa re pe: "Dajudaju owo inira ti kan mi. Iwo si ni Alaaanu julo ninu awon alaaanu
Author: Shaykh Abu Rahimah Mikael Aykyuni