ٱلۡمُلۡكُ يَوۡمَئِذٖ لِّلَّهِ يَحۡكُمُ بَيۡنَهُمۡۚ فَٱلَّذِينَ ءَامَنُواْ وَعَمِلُواْ ٱلصَّـٰلِحَٰتِ فِي جَنَّـٰتِ ٱلنَّعِيمِ
Gbogbo ijoba ojo yen n je ti Allahu ti O maa sedajo laaarin won. Nitori naa, awon t’o gbagbo ni ododo, ti won si se awon ise rere, (won yoo wa) ninu awon Ogba Idera
Author: Shaykh Abu Rahimah Mikael Aykyuni