Surah An-Noor Verse 62 - Yoruba Translation by Shaykh Abu Rahimah Mikael Aykyuni
Surah An-Noorإِنَّمَا ٱلۡمُؤۡمِنُونَ ٱلَّذِينَ ءَامَنُواْ بِٱللَّهِ وَرَسُولِهِۦ وَإِذَا كَانُواْ مَعَهُۥ عَلَىٰٓ أَمۡرٖ جَامِعٖ لَّمۡ يَذۡهَبُواْ حَتَّىٰ يَسۡتَـٔۡذِنُوهُۚ إِنَّ ٱلَّذِينَ يَسۡتَـٔۡذِنُونَكَ أُوْلَـٰٓئِكَ ٱلَّذِينَ يُؤۡمِنُونَ بِٱللَّهِ وَرَسُولِهِۦۚ فَإِذَا ٱسۡتَـٔۡذَنُوكَ لِبَعۡضِ شَأۡنِهِمۡ فَأۡذَن لِّمَن شِئۡتَ مِنۡهُمۡ وَٱسۡتَغۡفِرۡ لَهُمُ ٱللَّهَۚ إِنَّ ٱللَّهَ غَفُورٞ رَّحِيمٞ
Awon onigbagbo ni awon t’o gbagbo ninu Allahu ati Ojise Re. Nigba ti won ba si wa pelu re lori oro kan ti o kan gbogbogbo, won ko nii lo titi won yoo fi gba iyonda lodo re. Dajudaju awon t’o n gba iyonda lodo re, awon wonyen ni awon t’o gbagbo ninu Allahu ati Ojise Re. Nitori naa, ti won ba gba iyonda lodo re fun apa kan oro ara won, fun eni ti o ba fe ni iyonda ninu won, ki o si ba won toro aforijin lodo Allahu. Dajudaju Allahu ni Alaforijin, Asake-orun