Surah An-Naml Verse 40 - Yoruba Translation by Shaykh Abu Rahimah Mikael Aykyuni
Surah An-Namlقَالَ ٱلَّذِي عِندَهُۥ عِلۡمٞ مِّنَ ٱلۡكِتَٰبِ أَنَا۠ ءَاتِيكَ بِهِۦ قَبۡلَ أَن يَرۡتَدَّ إِلَيۡكَ طَرۡفُكَۚ فَلَمَّا رَءَاهُ مُسۡتَقِرًّا عِندَهُۥ قَالَ هَٰذَا مِن فَضۡلِ رَبِّي لِيَبۡلُوَنِيٓ ءَأَشۡكُرُ أَمۡ أَكۡفُرُۖ وَمَن شَكَرَ فَإِنَّمَا يَشۡكُرُ لِنَفۡسِهِۦۖ وَمَن كَفَرَ فَإِنَّ رَبِّي غَنِيّٞ كَرِيمٞ
Eni ti imo kan lati inu tira wa ni odo re so pe: “Emi yoo gbe e wa fun o siwaju ki o to seju.” Nigba ti o ri i ti o de si odo re, o so pe: “Eyi wa ninu oore ajulo Oluwa mi, lati fi dan mi wo boya mo maa dupe tabi mo maa sai moore. Enikeni ti o ba dupe (fun Allahu), o dupe fun emi ara re. Enikeni ti o ba si saimoore, dajudaju Oluwa mi ni Oloro, Alapon-onle.”