أَوَلَمۡ يَرَوۡاْ أَنَّ ٱللَّهَ يَبۡسُطُ ٱلرِّزۡقَ لِمَن يَشَآءُ وَيَقۡدِرُۚ إِنَّ فِي ذَٰلِكَ لَأٓيَٰتٖ لِّقَوۡمٖ يُؤۡمِنُونَ
Se won ko ri i pe dajudaju Allahu l’O n te oro sile fun eni ti O ba fe, (O si n) diwon re (fun eni ti O ba fe)? Dajudaju awon ami wa ninu iyen fun ijo t’o gbagbo
Author: Shaykh Abu Rahimah Mikael Aykyuni