Surah An-Nisa Verse 100 - Yoruba Translation by Shaykh Abu Rahimah Mikael Aykyuni
Surah An-Nisa۞وَمَن يُهَاجِرۡ فِي سَبِيلِ ٱللَّهِ يَجِدۡ فِي ٱلۡأَرۡضِ مُرَٰغَمٗا كَثِيرٗا وَسَعَةٗۚ وَمَن يَخۡرُجۡ مِنۢ بَيۡتِهِۦ مُهَاجِرًا إِلَى ٱللَّهِ وَرَسُولِهِۦ ثُمَّ يُدۡرِكۡهُ ٱلۡمَوۡتُ فَقَدۡ وَقَعَ أَجۡرُهُۥ عَلَى ٱللَّهِۗ وَكَانَ ٱللَّهُ غَفُورٗا رَّحِيمٗا
Enikeni ti o ba gbe ilu re ju sile nitori esin Allahu, o maa ri opolopo ibusasi ati igbalaaye lori ile. Enikeni ti o ba jade kuro ninu ile re (ti o je) olufilu-sile nitori esin Allahu ati Ojise Re, leyin naa ti iku ba a (loju ona), esan re kuku ti wa lodo Allahu. Allahu si n je Alaforijin, Asake-orun