Surah An-Nisa Verse 115 - Yoruba Translation by Shaykh Abu Rahimah Mikael Aykyuni
Surah An-Nisaوَمَن يُشَاقِقِ ٱلرَّسُولَ مِنۢ بَعۡدِ مَا تَبَيَّنَ لَهُ ٱلۡهُدَىٰ وَيَتَّبِعۡ غَيۡرَ سَبِيلِ ٱلۡمُؤۡمِنِينَ نُوَلِّهِۦ مَا تَوَلَّىٰ وَنُصۡلِهِۦ جَهَنَّمَۖ وَسَآءَتۡ مَصِيرًا
Enikeni ti o ba lodi si Ojise naa leyin ti imona ti foju han si i kedere, ti o tun tele ona t’o yato si ti awon onigbagbo ododo, A oo doju re ko ohun ti o doju ara re ko (ninu isina), A o si mu un wo inu ina Jahanamo. O si buru ni ikangun