Surah An-Nisa Verse 135 - Yoruba Translation by Shaykh Abu Rahimah Mikael Aykyuni
Surah An-Nisa۞يَـٰٓأَيُّهَا ٱلَّذِينَ ءَامَنُواْ كُونُواْ قَوَّـٰمِينَ بِٱلۡقِسۡطِ شُهَدَآءَ لِلَّهِ وَلَوۡ عَلَىٰٓ أَنفُسِكُمۡ أَوِ ٱلۡوَٰلِدَيۡنِ وَٱلۡأَقۡرَبِينَۚ إِن يَكُنۡ غَنِيًّا أَوۡ فَقِيرٗا فَٱللَّهُ أَوۡلَىٰ بِهِمَاۖ فَلَا تَتَّبِعُواْ ٱلۡهَوَىٰٓ أَن تَعۡدِلُواْۚ وَإِن تَلۡوُۥٓاْ أَوۡ تُعۡرِضُواْ فَإِنَّ ٱللَّهَ كَانَ بِمَا تَعۡمَلُونَ خَبِيرٗا
Eyin ti e gbagbo ni ododo, e je oluduro sinsin lori ododo nigba ti e ba n jerii nitori ti Allahu, koda ki (eri jije naa) tako eyin funra yin tabi awon obi mejeeji ati awon ebi; yala o je oloro tabi alaini. Allahu sunmo (yin) ju awon mejeeji lo. Nitori naa, e ma se tele ife-inu lati ma se deede. Ti e ba yi oju-oro sodi tabi ti e ba gbunri kuro (nibi deede), dajudaju Allahu n je Alamotan nipa ohun ti e n se nise