Surah An-Nisa Verse 150 - Yoruba Translation by Shaykh Abu Rahimah Mikael Aykyuni
Surah An-Nisaإِنَّ ٱلَّذِينَ يَكۡفُرُونَ بِٱللَّهِ وَرُسُلِهِۦ وَيُرِيدُونَ أَن يُفَرِّقُواْ بَيۡنَ ٱللَّهِ وَرُسُلِهِۦ وَيَقُولُونَ نُؤۡمِنُ بِبَعۡضٖ وَنَكۡفُرُ بِبَعۡضٖ وَيُرِيدُونَ أَن يَتَّخِذُواْ بَيۡنَ ذَٰلِكَ سَبِيلًا
Dajudaju awon t’o n sai gbagbo ninu Allahu ati awon Ojise Re, ti won fe sopinya laaarin Allahu ati awon Ojise Re, ti won si n wi pe: “A gbagbo ninu apa kan, a si sai gbagbo ninu apa kan,” won si fe mu ona kan to (lesin) laaarin iyen