Surah An-Nisa Verse 162 - Yoruba Translation by Shaykh Abu Rahimah Mikael Aykyuni
Surah An-Nisaلَّـٰكِنِ ٱلرَّـٰسِخُونَ فِي ٱلۡعِلۡمِ مِنۡهُمۡ وَٱلۡمُؤۡمِنُونَ يُؤۡمِنُونَ بِمَآ أُنزِلَ إِلَيۡكَ وَمَآ أُنزِلَ مِن قَبۡلِكَۚ وَٱلۡمُقِيمِينَ ٱلصَّلَوٰةَۚ وَٱلۡمُؤۡتُونَ ٱلزَّكَوٰةَ وَٱلۡمُؤۡمِنُونَ بِٱللَّهِ وَٱلۡيَوۡمِ ٱلۡأٓخِرِ أُوْلَـٰٓئِكَ سَنُؤۡتِيهِمۡ أَجۡرًا عَظِيمًا
Sugbon awon agba ninu imo ninu won ati awon onigbagbo ododo, won gbagbo ninu ohun ti A sokale fun o ati ohun ti A sokale siwaju re, (won tun gbagbo ninu awon molaika) t’o n kirun. (Awon wonyen) ati awon t’o n yo Zakah ati awon t’o gbagbo ninu Allahu ati Ojo Ikeyin, awon wonyen ni A maa fun ni esan nla