Surah An-Nisa Verse 63 - Yoruba Translation by Shaykh Abu Rahimah Mikael Aykyuni
Surah An-Nisaأُوْلَـٰٓئِكَ ٱلَّذِينَ يَعۡلَمُ ٱللَّهُ مَا فِي قُلُوبِهِمۡ فَأَعۡرِضۡ عَنۡهُمۡ وَعِظۡهُمۡ وَقُل لَّهُمۡ فِيٓ أَنفُسِهِمۡ قَوۡلَۢا بَلِيغٗا
Awon wonyen ni awon ti Allahu mo ohun ti n be ninu okan won. Nitori naa, seri kuro lodo won. Se waasi fun won, ki o si ba won so oro t’o lagbara nipa ara won