Surah An-Nisa Verse 76 - Yoruba Translation by Shaykh Abu Rahimah Mikael Aykyuni
Surah An-Nisaٱلَّذِينَ ءَامَنُواْ يُقَٰتِلُونَ فِي سَبِيلِ ٱللَّهِۖ وَٱلَّذِينَ كَفَرُواْ يُقَٰتِلُونَ فِي سَبِيلِ ٱلطَّـٰغُوتِ فَقَٰتِلُوٓاْ أَوۡلِيَآءَ ٱلشَّيۡطَٰنِۖ إِنَّ كَيۡدَ ٱلشَّيۡطَٰنِ كَانَ ضَعِيفًا
Awon t’o gbagbo ni ododo n jagun fun esin Allahu. Awon t’o sai gbagbo si n jagun fun esin orisa. Nitori naa, e ja awon ore Esu logun. Dajudaju ete Esu, o je ohun ti o le