فَإِن كَذَّبُوكَ فَقُل رَّبُّكُمۡ ذُو رَحۡمَةٖ وَٰسِعَةٖ وَلَا يُرَدُّ بَأۡسُهُۥ عَنِ ٱلۡقَوۡمِ ٱلۡمُجۡرِمِينَ
Tí wọ́n bá sì pè ọ́ ní òpùrọ́, sọ nígbà náà pé: "Olúwa yín ni Oníkẹ̀ẹ́ tó gbòòrò. Kò sì sí ẹni t’ó lè gbé ìyà Rẹ̀ kúrò lórí ìjọ ẹlẹ́ṣẹ̀
Author: Shaykh Abu Rahimah Mikael Aykyuni