۞إِنَّمَا يَسۡتَجِيبُ ٱلَّذِينَ يَسۡمَعُونَۘ وَٱلۡمَوۡتَىٰ يَبۡعَثُهُمُ ٱللَّهُ ثُمَّ إِلَيۡهِ يُرۡجَعُونَ
Àwọn t’ó ń gbọ́rọ̀ ni àwọn t’ó ń jẹ́pè. Àwọn òkú, Allāhu yó sì gbé wọn dìde. Lẹ́yìn náà, ọ̀dọ̀ Rẹ̀ ni wọn yóò dá wọn padà sí
Author: Shaykh Abu Rahimah Mikael Aykyuni