Surah Al-Araf Verse 23 - Yoruba Translation by Shaykh Abu Rahimah Mikael Aykyuni
Surah Al-Arafقَالَا رَبَّنَا ظَلَمۡنَآ أَنفُسَنَا وَإِن لَّمۡ تَغۡفِرۡ لَنَا وَتَرۡحَمۡنَا لَنَكُونَنَّ مِنَ ٱلۡخَٰسِرِينَ
Awon mejeeji so pe: "Oluwa wa, a ti sabosi si emi wa. Ti O o ba forijin wa, ki O si ke wa, dajudaju a maa wa ninu awon eni ofo." gege bi won tun se gbagbo pe eje Anabi ‘Isa omo Moryam ('alaehi-ssolatu wa-ssalam) lori igi agbelebuu ti pa awon ese miiran re fun gbogbo awon t’o gbagbo ninu Jesu Kristi ati eje re lori igi agbelebuu. Allahu si so pe eleru-ese kan ko nii ru eru-ese elomiiran mo tire. Ikerin; awon kristieni di olusina nipa bi won se so Anabi ‘Isa omo Moryam ati iya re di olohun ti won n josin fun nitori pe won gba pe ikini keji won nikan ni ko ni egun ese eso jije lorun ati pe won tun gbagbo pe Hawa’ (rodiyallahu 'anha) je eso igi naa. Jije re si je ese lorun awon mejeeji nikan ko si ese eso jije lorun awon omo won kan kan. Koko keji: awon mejeeji toro aforijin lori asise naa ti won si so gbogbo omo re di elese eso nipase re ohun ni pe