وَمَآ أَرۡسَلۡنَا فِي قَرۡيَةٖ مِّن نَّبِيٍّ إِلَّآ أَخَذۡنَآ أَهۡلَهَا بِٱلۡبَأۡسَآءِ وَٱلضَّرَّآءِ لَعَلَّهُمۡ يَضَّرَّعُونَ
A o ran Anabi kan si ilu kan lai je pe A fi iponju ati inira kan awon ara ilu naa nitori ki won le rawo-rase (si Allahu)
Author: Shaykh Abu Rahimah Mikael Aykyuni