Surah Al-Anfal Verse 70 - Yoruba Translation by Shaykh Abu Rahimah Mikael Aykyuni
Surah Al-Anfalيَـٰٓأَيُّهَا ٱلنَّبِيُّ قُل لِّمَن فِيٓ أَيۡدِيكُم مِّنَ ٱلۡأَسۡرَىٰٓ إِن يَعۡلَمِ ٱللَّهُ فِي قُلُوبِكُمۡ خَيۡرٗا يُؤۡتِكُمۡ خَيۡرٗا مِّمَّآ أُخِذَ مِنكُمۡ وَيَغۡفِرۡ لَكُمۡۚ وَٱللَّهُ غَفُورٞ رَّحِيمٞ
Iwo Anabi, so fun awon t’o n be lowo yin ninu awon eru ogun pe, “Ti Allahu ba mo daadaa kan ninu okan yin, O maa fun yin ni ohun t’o dara ju ohun ti won gba lowo yin. O si maa forijin yin. Allahu si ni Alaforijin, Onikee.”