Surah At-Taubah Verse 111 - Yoruba Translation by Shaykh Abu Rahimah Mikael Aykyuni
Surah At-Taubah۞إِنَّ ٱللَّهَ ٱشۡتَرَىٰ مِنَ ٱلۡمُؤۡمِنِينَ أَنفُسَهُمۡ وَأَمۡوَٰلَهُم بِأَنَّ لَهُمُ ٱلۡجَنَّةَۚ يُقَٰتِلُونَ فِي سَبِيلِ ٱللَّهِ فَيَقۡتُلُونَ وَيُقۡتَلُونَۖ وَعۡدًا عَلَيۡهِ حَقّٗا فِي ٱلتَّوۡرَىٰةِ وَٱلۡإِنجِيلِ وَٱلۡقُرۡءَانِۚ وَمَنۡ أَوۡفَىٰ بِعَهۡدِهِۦ مِنَ ٱللَّهِۚ فَٱسۡتَبۡشِرُواْ بِبَيۡعِكُمُ ٱلَّذِي بَايَعۡتُم بِهِۦۚ وَذَٰلِكَ هُوَ ٱلۡفَوۡزُ ٱلۡعَظِيمُ
Dajudaju Allahu ra emi awon onigbagbo ododo ati dukia won nitori pe dajudaju tiwon ni Ogba Idera. Won n jagun loju ona (esin) Allahu; won n pa ota esin, won si n pa awon naa. (O je) adehun lodo Allahu. (O je) ododo ninu at-Taorah, al-’Injil ati al-Ƙur’an. Ta si ni o le mu adehun re se ju Allahu? Nitori naa, e dunnu si okowo yin ti e (fi emi ati dukia yin) se. Iyen, ohun si ni erenje nla