Surah An-Nisa Verse 56 - Yoruba Translation by Shaykh Abu Rahimah Mikael Aykyuni
Surah An-Nisaإِنَّ ٱلَّذِينَ كَفَرُواْ بِـَٔايَٰتِنَا سَوۡفَ نُصۡلِيهِمۡ نَارٗا كُلَّمَا نَضِجَتۡ جُلُودُهُم بَدَّلۡنَٰهُمۡ جُلُودًا غَيۡرَهَا لِيَذُوقُواْ ٱلۡعَذَابَۗ إِنَّ ٱللَّهَ كَانَ عَزِيزًا حَكِيمٗا
Dajudaju awon t’o sai gbagbo ninu awon ayah Wa, laipe A maa mu won wo inu Ina. Igbakigba ti awo ara won ba jona, A oo maa paaro awo ara miiran fun won ki won le maa to iya wo lo. Dajudaju Allahu n je Alagbara, Ologbon