Surah An-Nisa Verse 57 - Yoruba Translation by Shaykh Abu Rahimah Mikael Aykyuni
Surah An-Nisaوَٱلَّذِينَ ءَامَنُواْ وَعَمِلُواْ ٱلصَّـٰلِحَٰتِ سَنُدۡخِلُهُمۡ جَنَّـٰتٖ تَجۡرِي مِن تَحۡتِهَا ٱلۡأَنۡهَٰرُ خَٰلِدِينَ فِيهَآ أَبَدٗاۖ لَّهُمۡ فِيهَآ أَزۡوَٰجٞ مُّطَهَّرَةٞۖ وَنُدۡخِلُهُمۡ ظِلّٗا ظَلِيلًا
Awon t’o gbagbo ni ododo, ti won si se awon ise rere, A oo mu won wo inu awon Ogba Idera kan, ti awon odo n san ni isale re. Olusegbere ni won ninu re titi laelae. Awon iyawo mimo n be fun won ninu re. A si maa fi won si abe iboji t’o maa siji bo won daradara