Surah An-Nisa Verse 60 - Yoruba Translation by Shaykh Abu Rahimah Mikael Aykyuni
Surah An-Nisaأَلَمۡ تَرَ إِلَى ٱلَّذِينَ يَزۡعُمُونَ أَنَّهُمۡ ءَامَنُواْ بِمَآ أُنزِلَ إِلَيۡكَ وَمَآ أُنزِلَ مِن قَبۡلِكَ يُرِيدُونَ أَن يَتَحَاكَمُوٓاْ إِلَى ٱلطَّـٰغُوتِ وَقَدۡ أُمِرُوٓاْ أَن يَكۡفُرُواْ بِهِۦۖ وَيُرِيدُ ٱلشَّيۡطَٰنُ أَن يُضِلَّهُمۡ ضَلَٰلَۢا بَعِيدٗا
Se o o ri awon t’o n soro (ti ko si ri bee) pe dajudaju awon gbagbo ninu ohun ti A sokale fun o ati ohun ti A sokale siwaju re, ti won si n gbero lati gbe ejo lo ba orisa, A si ti pa won lase pe ki won lodi si i. Esu si fe si won lona ni isina t’o jinna