وَإِذَا قِيلَ لَهُمۡ تَعَالَوۡاْ إِلَىٰ مَآ أَنزَلَ ٱللَّهُ وَإِلَى ٱلرَّسُولِ رَأَيۡتَ ٱلۡمُنَٰفِقِينَ يَصُدُّونَ عَنكَ صُدُودٗا
Nigba ti won ba so fun won pe: “E wa sibi ohun ti Allahu sokale, e wa ba Ojise.”, o maa ri awon munaafiki ti won yoo maa seri kuro lodo re taara
Author: Shaykh Abu Rahimah Mikael Aykyuni