وَذَرُواْ ظَٰهِرَ ٱلۡإِثۡمِ وَبَاطِنَهُۥٓۚ إِنَّ ٱلَّذِينَ يَكۡسِبُونَ ٱلۡإِثۡمَ سَيُجۡزَوۡنَ بِمَا كَانُواْ يَقۡتَرِفُونَ
Ẹ fi èyí t’ó hàn nínú ẹ̀ṣẹ̀ àti èyí t’ó pamọ́ nínú rẹ̀ sílẹ̀. Dájúdájú àwọn t’ó ń ṣe iṣẹ́ ẹ̀ṣẹ̀, A óò san wọ́n ní ẹ̀san ohun tí wọ́n ń dá lẹ́ṣẹ̀
Author: Shaykh Abu Rahimah Mikael Aykyuni